Exodus 24 (BOYCB)
1 Ní ìgbà náà ni OLÚWA sọ fún Mose pé, “Gòkè tọ OLÚWA wá, ìwọ àti Aaroni, Nadabu àti Abihu àti àádọ́rin àwọn àgbàgbà Israẹli. Ẹ̀yin kì ó sìn ni òkèèrè réré. 2 Ṣùgbọ́n Mose nìkan ṣoṣo ni yóò súnmọ́ OLÚWA; àwọn tókù kò gbọdọ̀ súnmọ́ tòsí ibẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn kò gbọdọ̀ gòkè wá pẹ̀lú rẹ̀.” 3 Nígbà ti Mose lọ láti sọ fún àwọn ènìyàn, gbogbo ọ̀rọ̀ àti òfin OLÚWA, wọ́n wí ní ohùn kan pé, “Gbogbo ohun ti OLÚWA wí ni àwa yóò ṣe.” 4 Nígbà náà ni Mose kọ gbogbo ohun tí OLÚWA sọ sílẹ̀.Ó dìde ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó sì mọ pẹpẹ ni ẹsẹ̀ òkè náà. Ó ṣe ọ̀wọ́n òkúta méjìlá. Èyí ti ó dúró fún àwọn ẹ̀yà Israẹli méjìlá. 5 Nígbà náà ni ó rán àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin Israẹli, wọ́n sì rú ẹbọ sísun, wọ́n fi ọ̀dọ́ màlúù rú ẹbọ àlàáfíà si OLÚWA. 6 Mose bu ìlàjì ẹ̀jẹ̀ ẹran sínú abọ́, ó sì fi ìlàjì tókù wọn ara pẹpẹ. 7 Nígbà náà ni ó sì mú ìwé májẹ̀mú, ó sì kà á sí àwọn ènìyàn. Wọ́n dáhùn pé, “Àwa yóò ṣe gbogbo ohun tí OLÚWA wí. Àwa yóò sì gbọ́rọ̀.” 8 Nígbà náà ni Mose gbé ẹ̀jẹ̀, ó sì wọn sí àwọn ènìyàn náà lára pé, “Èyí ni ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú tí OLÚWA ti ṣe pẹ̀lú yín ni ìbámu pẹ̀lú àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí.” 9 Mose àti Aaroni, Nadabu àti Abihu àti àádọ́rin àwọn àgbàgbà Israẹli gòkè lọ. 10 Wọ́n sì rí Ọlọ́run Israẹli. Ní abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀ ni ohun kan bí i pèpéle ti a fi òkúta safire ṣe wà. Èyí ti ó mọ́ nigínnigín bí àwọ̀ sánmọ̀ fúnra rẹ̀. 11 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kò gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè sí àwọn àgbàgbà Israẹli wọ̀nyí; wọ́n ri Ọlọ́run, wọ́n jẹ, wọ́n sì mu. 12 OLÚWA sì sọ fún Mose pé, “Gòkè wá sí ọ̀dọ̀ mi, kí o sì dúró níhìn-ín. Èmi yóò sì fún ọ ní wàláà òkúta pẹ̀lú òfin àti ìlànà tí mo ti kọ sílẹ̀ fún ìtọ́sọ́nà wọn.” 13 Nígbà náà ni Mose jáde lọ pẹ̀lú Joṣua arákùnrin rẹ̀. Mose lọ sí orí òkè Ọlọ́run. 14 Ó sì wí fún àwọn àgbàgbà pé, “Ẹ dúró dè wá níhìn-ín yìí, títí àwa yóò fi tún padà tọ̀ yín wá, sì kíyèsi i, Aaroni àti Huri ń bẹ pẹ̀lú yín, bí ẹnìkan bá ni ọ̀ràn kan, kí ó tọ̀ wọ́n lọ.” 15 Nígbà tí Mose gun orí òkè lọ, ìkùùkuu bo orí òkè náà. 16 Ògo OLÚWA sì wà ní orí òkè Sinai. Ìkùùkuu bo orí òkè náà fún ọjọ́ mẹ́fà, ni ọjọ́ keje ni OLÚWA kọ sí Mose láti inú ìkùùkuu náà wá. 17 Ni ojú àwọn ọmọ Israẹli ògo OLÚWA náà dàbí iná ajónirun ni orí òkè. 18 Nígbà náà ni Mose wọ inú ìkùùkuu náà bí ó ti ń lọ ní orí òkè. Ó sì wà ni orí òkè náà ni ogójì ọ̀sán àti ogójì òru.
In Other Versions
Exodus 24 in the ANGEFD
Exodus 24 in the ANTPNG2D
Exodus 24 in the AS21
Exodus 24 in the BAGH
Exodus 24 in the BBPNG
Exodus 24 in the BBT1E
Exodus 24 in the BDS
Exodus 24 in the BEV
Exodus 24 in the BHAD
Exodus 24 in the BIB
Exodus 24 in the BLPT
Exodus 24 in the BNT
Exodus 24 in the BNTABOOT
Exodus 24 in the BNTLV
Exodus 24 in the BOATCB
Exodus 24 in the BOATCB2
Exodus 24 in the BOBCV
Exodus 24 in the BOCNT
Exodus 24 in the BOECS
Exodus 24 in the BOGWICC
Exodus 24 in the BOHCB
Exodus 24 in the BOHCV
Exodus 24 in the BOHLNT
Exodus 24 in the BOHNTLTAL
Exodus 24 in the BOICB
Exodus 24 in the BOILNTAP
Exodus 24 in the BOITCV
Exodus 24 in the BOKCV
Exodus 24 in the BOKCV2
Exodus 24 in the BOKHWOG
Exodus 24 in the BOKSSV
Exodus 24 in the BOLCB
Exodus 24 in the BOLCB2
Exodus 24 in the BOMCV
Exodus 24 in the BONAV
Exodus 24 in the BONCB
Exodus 24 in the BONLT
Exodus 24 in the BONUT2
Exodus 24 in the BOPLNT
Exodus 24 in the BOSCB
Exodus 24 in the BOSNC
Exodus 24 in the BOTLNT
Exodus 24 in the BOVCB
Exodus 24 in the BPBB
Exodus 24 in the BPH
Exodus 24 in the BSB
Exodus 24 in the CCB
Exodus 24 in the CUV
Exodus 24 in the CUVS
Exodus 24 in the DBT
Exodus 24 in the DGDNT
Exodus 24 in the DHNT
Exodus 24 in the DNT
Exodus 24 in the ELBE
Exodus 24 in the EMTV
Exodus 24 in the ESV
Exodus 24 in the FBV
Exodus 24 in the FEB
Exodus 24 in the GGMNT
Exodus 24 in the GNT
Exodus 24 in the HARY
Exodus 24 in the HNT
Exodus 24 in the IRVA
Exodus 24 in the IRVB
Exodus 24 in the IRVG
Exodus 24 in the IRVH
Exodus 24 in the IRVK
Exodus 24 in the IRVM
Exodus 24 in the IRVM2
Exodus 24 in the IRVO
Exodus 24 in the IRVP
Exodus 24 in the IRVT
Exodus 24 in the IRVT2
Exodus 24 in the IRVU
Exodus 24 in the ISVN
Exodus 24 in the JSNT
Exodus 24 in the KAPI
Exodus 24 in the KBT1ETNIK
Exodus 24 in the KBV
Exodus 24 in the KJV
Exodus 24 in the KNFD
Exodus 24 in the LBA
Exodus 24 in the LBLA
Exodus 24 in the LNT
Exodus 24 in the LSV
Exodus 24 in the MAAL
Exodus 24 in the MBV
Exodus 24 in the MBV2
Exodus 24 in the MHNT
Exodus 24 in the MKNFD
Exodus 24 in the MNG
Exodus 24 in the MNT
Exodus 24 in the MNT2
Exodus 24 in the MRS1T
Exodus 24 in the NAA
Exodus 24 in the NASB
Exodus 24 in the NBLA
Exodus 24 in the NBS
Exodus 24 in the NBVTP
Exodus 24 in the NET2
Exodus 24 in the NIV11
Exodus 24 in the NNT
Exodus 24 in the NNT2
Exodus 24 in the NNT3
Exodus 24 in the PDDPT
Exodus 24 in the PFNT
Exodus 24 in the RMNT
Exodus 24 in the SBIAS
Exodus 24 in the SBIBS
Exodus 24 in the SBIBS2
Exodus 24 in the SBICS
Exodus 24 in the SBIDS
Exodus 24 in the SBIGS
Exodus 24 in the SBIHS
Exodus 24 in the SBIIS
Exodus 24 in the SBIIS2
Exodus 24 in the SBIIS3
Exodus 24 in the SBIKS
Exodus 24 in the SBIKS2
Exodus 24 in the SBIMS
Exodus 24 in the SBIOS
Exodus 24 in the SBIPS
Exodus 24 in the SBISS
Exodus 24 in the SBITS
Exodus 24 in the SBITS2
Exodus 24 in the SBITS3
Exodus 24 in the SBITS4
Exodus 24 in the SBIUS
Exodus 24 in the SBIVS
Exodus 24 in the SBT
Exodus 24 in the SBT1E
Exodus 24 in the SCHL
Exodus 24 in the SNT
Exodus 24 in the SUSU
Exodus 24 in the SUSU2
Exodus 24 in the SYNO
Exodus 24 in the TBIAOTANT
Exodus 24 in the TBT1E
Exodus 24 in the TBT1E2
Exodus 24 in the TFTIP
Exodus 24 in the TFTU
Exodus 24 in the TGNTATF3T
Exodus 24 in the THAI
Exodus 24 in the TNFD
Exodus 24 in the TNT
Exodus 24 in the TNTIK
Exodus 24 in the TNTIL
Exodus 24 in the TNTIN
Exodus 24 in the TNTIP
Exodus 24 in the TNTIZ
Exodus 24 in the TOMA
Exodus 24 in the TTENT
Exodus 24 in the UBG
Exodus 24 in the UGV
Exodus 24 in the UGV2
Exodus 24 in the UGV3
Exodus 24 in the VBL
Exodus 24 in the VDCC
Exodus 24 in the YALU
Exodus 24 in the YAPE
Exodus 24 in the YBVTP
Exodus 24 in the ZBP