Nehemiah 6 (BOYCB)

1 Nígbà tí Sanballati, Tobiah Geṣemu ará Arabia àti àwọn ọ̀tá wa tókù gbọ́ pé, mo ti tún odi náà mọ, kò sì sí àlàfo kankan tí ó ṣẹ́kù nínú rẹ̀—bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé èmi kò ì tí ì ri àwọn ìlẹ̀kùn ibodè ní àkókò náà. 2 Sanballati àti Geṣemu rán iṣẹ́ yìí sí mi pé, “Wá jẹ́ kí a jọ pàdé pọ̀ nínú ọ̀kan lára àwọn ìletò ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Ono.”Ṣùgbọ́n wọ́n ń gbèrò láti ṣe mí ní ibi; 3 bẹ́ẹ̀ ni mo rán oníṣẹ́ padà pẹ̀lú èsì yìí pé, “Èmi ń ṣe iṣẹ́ ńlá kan, èmi kò le è sọ̀kalẹ̀ wá. Èéṣe tí iṣẹ́ náà yóò fi dúró, nígbà tí mo bá fi í sílẹ̀ tí mo sì sọ̀kalẹ̀ tọ̀ yín wá?” 4 Wọ́n rán iṣẹ́ náà sí mi nígbà mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, mo sì fún wọn ní èsì bákan náà fún ìgbà kọ̀ọ̀kan. 5 Ní ìgbà karùn-ún, Sanballati rán ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ sí mi pẹ̀lú irú iṣẹ́ kan náà, lẹ́tà kan tí a kò fi sínú àpò ìwé wà ní ọwọ́ rẹ̀ 6 tí a kọ sínú un rẹ̀ pé,“A ròyìn rẹ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, Geṣemu sì sọ pé, òtítọ́ ni, pé ìwọ àti àwọn Júù ń gbèrò láti ṣọ̀tẹ̀, nítorí náà ni ẹ ṣe ń mọ odi. Síwájú sí i, gẹ́gẹ́ bí ìròyìn yìí, ìwọ sì ń gbèrò láti di ọba wọn 7 àti pé ó ti yan àwọn wòlíì kí wọn lè kéde nípa rẹ̀ ní Jerusalẹmu: ‘Ọba kan wà ní Juda!’ Nísinsin yìí, ìròyìn yìí yóò padà sí ọ̀dọ̀ ọba; nítorí náà wá, jẹ́ kí a bá ara wa sọ̀rọ̀.” 8 Mo dá èsì yìí padà sí i pé, “Kò sí ohun kan nínú irú ohun tí ìwọ sọ tí ó ṣẹlẹ̀; ìwọ kàn rò wọ́n ní orí ara rẹ ni.” 9 Gbogbo wọn múra láti dẹ́rùbà wá, wọ́n ń rò ó wí pé, “Ọwọ́ wọn kò ní ran iṣẹ́ náà, àti wí pé wọn kò ní parí rẹ̀.”Ṣùgbọ́n mo gbàdúrà pé, “Nísinsin yìí Ọlọ́run fi agbára fún ọwọ́ mi.” 10 Ní ọjọ́ kan mo lọ sí ilé Ṣemaiah ọmọ Delaiah, ọmọ Mehetabeeli, ẹni tí a há mọ́ sínú ilé rẹ̀. Ó wí pé, “Jẹ́ kí a pàdé ní ilé Ọlọ́run nínú tẹmpili, kí o sì jẹ́ kí a pa àwọn ìlẹ̀kùn tẹmpili dé, nítorí àwọn ènìyàn ń bọ̀ láti pa ọ́, ní òru ni wọn yóò wá láti pa ọ́.” 11 Ṣùgbọ́n mo wí pé, “Ǹjẹ́ ó yẹ kí irú ènìyàn bí èmi sálọ? Tàbí kí ènìyàn bí èmi sálọ sínú tẹmpili láti gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là? Èmi kò ní lọ!” 12 Èmi wòye pé Ọlọ́run kò rán an, ṣùgbọ́n ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí mi nítorí Tobiah àti Sanballati ti bẹ̀ ẹ́ ní ọ̀wẹ̀. 13 Wọ́n bẹ̀ ẹ́ ní ọ̀wẹ̀ láti dẹ́rùbà mí nítorí kí èmi lè dẹ́ṣẹ̀ nípa ṣíṣe èyí, kí wọn lè bà mí lórúkọ jẹ́, kí n sì di ẹni ẹ̀gàn. 14 A! Ọlọ́run mi, rántí Tobiah àti Sanballati, nítorí ohun tí wọ́n ti ṣe; kí o sì tún rántí Noadiah wòlíì obìnrin àti àwọn wòlíì tókù tí wọ́n ń gbèrò láti dẹ́rùbà mí. 15 Bẹ́ẹ̀ ni a parí odi náà ní ọjọ́ kẹẹdọ́gbọ̀n oṣù Eluli, láàrín ọjọ́ méjìléláàádọ́ta. 16 Nígbà tí àwọn ọ̀tá wa gbọ́ èyí, gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí wa ká bẹ̀rù jìnnìjìnnì sì mú wọn, nítorí wọ́n wòye pé iṣẹ́ yìí di ṣíṣe pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Ọlọ́run wa. 17 Bákan náà, ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ọlọ́lá Juda ń kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ lẹ́tà ránṣẹ́ sí Tobiah, èsì láti ọ̀dọ̀ Tobiah sì ń wá sí ọ̀dọ̀ wọn. 18 Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Juda ti mulẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀, nítorí tí ó jẹ́ àna Ṣekaniah ọmọ Arah (Sanballati fẹ́ ọmọ Ṣekaniah), ọmọ rẹ̀ Jehohanani sì tún fẹ́ ọmọbìnrin Meṣullamu ọmọ Berekiah. 19 Síwájú sí í, wọ́n túbọ̀ ń ròyìn iṣẹ́ rere rẹ̀ fún mi, wọ́n sì ń sọ ohun tí mo sọ fún un. Tobiah sì ń kọ àwọn lẹ́tà ránṣẹ́ sí mi láti dẹ́rùbà mí.

In Other Versions

Nehemiah 6 in the ANGEFD

Nehemiah 6 in the ANTPNG2D

Nehemiah 6 in the AS21

Nehemiah 6 in the BAGH

Nehemiah 6 in the BBPNG

Nehemiah 6 in the BBT1E

Nehemiah 6 in the BDS

Nehemiah 6 in the BEV

Nehemiah 6 in the BHAD

Nehemiah 6 in the BIB

Nehemiah 6 in the BLPT

Nehemiah 6 in the BNT

Nehemiah 6 in the BNTABOOT

Nehemiah 6 in the BNTLV

Nehemiah 6 in the BOATCB

Nehemiah 6 in the BOATCB2

Nehemiah 6 in the BOBCV

Nehemiah 6 in the BOCNT

Nehemiah 6 in the BOECS

Nehemiah 6 in the BOGWICC

Nehemiah 6 in the BOHCB

Nehemiah 6 in the BOHCV

Nehemiah 6 in the BOHLNT

Nehemiah 6 in the BOHNTLTAL

Nehemiah 6 in the BOICB

Nehemiah 6 in the BOILNTAP

Nehemiah 6 in the BOITCV

Nehemiah 6 in the BOKCV

Nehemiah 6 in the BOKCV2

Nehemiah 6 in the BOKHWOG

Nehemiah 6 in the BOKSSV

Nehemiah 6 in the BOLCB

Nehemiah 6 in the BOLCB2

Nehemiah 6 in the BOMCV

Nehemiah 6 in the BONAV

Nehemiah 6 in the BONCB

Nehemiah 6 in the BONLT

Nehemiah 6 in the BONUT2

Nehemiah 6 in the BOPLNT

Nehemiah 6 in the BOSCB

Nehemiah 6 in the BOSNC

Nehemiah 6 in the BOTLNT

Nehemiah 6 in the BOVCB

Nehemiah 6 in the BPBB

Nehemiah 6 in the BPH

Nehemiah 6 in the BSB

Nehemiah 6 in the CCB

Nehemiah 6 in the CUV

Nehemiah 6 in the CUVS

Nehemiah 6 in the DBT

Nehemiah 6 in the DGDNT

Nehemiah 6 in the DHNT

Nehemiah 6 in the DNT

Nehemiah 6 in the ELBE

Nehemiah 6 in the EMTV

Nehemiah 6 in the ESV

Nehemiah 6 in the FBV

Nehemiah 6 in the FEB

Nehemiah 6 in the GGMNT

Nehemiah 6 in the GNT

Nehemiah 6 in the HARY

Nehemiah 6 in the HNT

Nehemiah 6 in the IRVA

Nehemiah 6 in the IRVB

Nehemiah 6 in the IRVG

Nehemiah 6 in the IRVH

Nehemiah 6 in the IRVK

Nehemiah 6 in the IRVM

Nehemiah 6 in the IRVM2

Nehemiah 6 in the IRVO

Nehemiah 6 in the IRVP

Nehemiah 6 in the IRVT

Nehemiah 6 in the IRVT2

Nehemiah 6 in the IRVU

Nehemiah 6 in the ISVN

Nehemiah 6 in the JSNT

Nehemiah 6 in the KAPI

Nehemiah 6 in the KBT1ETNIK

Nehemiah 6 in the KBV

Nehemiah 6 in the KJV

Nehemiah 6 in the KNFD

Nehemiah 6 in the LBA

Nehemiah 6 in the LBLA

Nehemiah 6 in the LNT

Nehemiah 6 in the LSV

Nehemiah 6 in the MAAL

Nehemiah 6 in the MBV

Nehemiah 6 in the MBV2

Nehemiah 6 in the MHNT

Nehemiah 6 in the MKNFD

Nehemiah 6 in the MNG

Nehemiah 6 in the MNT

Nehemiah 6 in the MNT2

Nehemiah 6 in the MRS1T

Nehemiah 6 in the NAA

Nehemiah 6 in the NASB

Nehemiah 6 in the NBLA

Nehemiah 6 in the NBS

Nehemiah 6 in the NBVTP

Nehemiah 6 in the NET2

Nehemiah 6 in the NIV11

Nehemiah 6 in the NNT

Nehemiah 6 in the NNT2

Nehemiah 6 in the NNT3

Nehemiah 6 in the PDDPT

Nehemiah 6 in the PFNT

Nehemiah 6 in the RMNT

Nehemiah 6 in the SBIAS

Nehemiah 6 in the SBIBS

Nehemiah 6 in the SBIBS2

Nehemiah 6 in the SBICS

Nehemiah 6 in the SBIDS

Nehemiah 6 in the SBIGS

Nehemiah 6 in the SBIHS

Nehemiah 6 in the SBIIS

Nehemiah 6 in the SBIIS2

Nehemiah 6 in the SBIIS3

Nehemiah 6 in the SBIKS

Nehemiah 6 in the SBIKS2

Nehemiah 6 in the SBIMS

Nehemiah 6 in the SBIOS

Nehemiah 6 in the SBIPS

Nehemiah 6 in the SBISS

Nehemiah 6 in the SBITS

Nehemiah 6 in the SBITS2

Nehemiah 6 in the SBITS3

Nehemiah 6 in the SBITS4

Nehemiah 6 in the SBIUS

Nehemiah 6 in the SBIVS

Nehemiah 6 in the SBT

Nehemiah 6 in the SBT1E

Nehemiah 6 in the SCHL

Nehemiah 6 in the SNT

Nehemiah 6 in the SUSU

Nehemiah 6 in the SUSU2

Nehemiah 6 in the SYNO

Nehemiah 6 in the TBIAOTANT

Nehemiah 6 in the TBT1E

Nehemiah 6 in the TBT1E2

Nehemiah 6 in the TFTIP

Nehemiah 6 in the TFTU

Nehemiah 6 in the TGNTATF3T

Nehemiah 6 in the THAI

Nehemiah 6 in the TNFD

Nehemiah 6 in the TNT

Nehemiah 6 in the TNTIK

Nehemiah 6 in the TNTIL

Nehemiah 6 in the TNTIN

Nehemiah 6 in the TNTIP

Nehemiah 6 in the TNTIZ

Nehemiah 6 in the TOMA

Nehemiah 6 in the TTENT

Nehemiah 6 in the UBG

Nehemiah 6 in the UGV

Nehemiah 6 in the UGV2

Nehemiah 6 in the UGV3

Nehemiah 6 in the VBL

Nehemiah 6 in the VDCC

Nehemiah 6 in the YALU

Nehemiah 6 in the YAPE

Nehemiah 6 in the YBVTP

Nehemiah 6 in the ZBP