Ezekiel 24 (BOYCB)

1 Ní ọdún kẹsànán, oṣù kẹwàá, ọjọ́ kẹwàá, ni ọ̀rọ̀ OLÚWA tọ̀ mí wá wí pé: 2 “Ọmọ ènìyàn, kọ ọjọ́ náà sílẹ̀, ọjọ́ náà gan an, nítorí ọba Babeli náà ti da ojú ti Jerusalẹmu ní ọjọ́ yìí gan an. 3 Sì pa òwe yìí fún ilé ọlọ́tẹ̀ náà, sọ fún wọn pé: ‘Èyí yìí ni OLÚWA Olódùmarè wí:“ ‘Gbé ìkòkò ìdáná náà ka iná,gbé e ka iná kí o sì da omi sí i nínú. 4 Kó àwọn ègé ẹran tí a gé náà sínú rẹ̀,gbogbo àwọn ègé ẹran tí ó tóbi, itan àti apá.Kó àwọn egungun tí ó dára jù sínú rẹ̀, 5 mú àwọn tí ó jọjú nínú agbo ẹran.Kó àwọn egungun sí abẹ́ ẹ rẹ̀;sì jẹ́ kí ó hó dáradárasì jẹ́ kí àwọn egungun náà bọ̀ nínú rẹ̀. 6 Nítorí báyìí ní OLÚWA Olódùmarè wí:“ ‘Ègbé ni fún ìlú ẹlẹ́jẹ̀ náà,fún ìkòkò náà tí èérí rẹ̀ wà nínú rẹ̀,tí èérí kò dà kúrò lójú rẹ̀!Mú ẹran náà jáde ní ekìrí ekìrímá ṣe ṣà wọ́n mú. 7 “ ‘Nítorí ẹ̀jẹ̀ tí ó ta sílẹ̀ wà ní àárín rẹ̀;à á sí orí àpáta kan lásánkò dà á sí orí ilẹ̀,níbi ti erùpẹ̀ yóò ti bò ó. 8 Láti bá à le jẹ́ kí ìbínú kí ó dé láti gbẹ̀sanmo da ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sí orí àpáta kan lásán,kí o ma bà á wà ni bíbò. 9 Nítorí náà báyìí ni OLÚWA Olódùmarè wí:“ ‘Ègbé ni fún ìlú ẹlẹ́jẹ̀ náà!Èmi pàápàá yóò jẹ́ kí òkìtì iná náà tóbi. 10 Nítorí náà kó igi náà jọ sí i,kí o sì fi iná sí i.Ṣe ẹran náà dáradára,fi tùràrí dùn ún;kí o sì jẹ́ kí egungun náà jóná. 11 Lẹ́yìn náà gbé òfìfo ìkòkò náà lórí ẹyin inákí idẹ rẹ̀ lè gbóná, kí ó lè pọ́nàti ki ìfófó rẹ̀ le di yíyọ́ nínú rẹ̀kí èérí rẹ̀ le jó dànù. 12 Ó ti ba gbogbo akitiyan jẹ:èérí rẹ̀ kò sì jáde kúrò lára rẹ̀,èérí náà gan an yóò wà nínú iná. 13 “ ‘Nísinsin yìí èérí rẹ̀ ni ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wà. Nítorí mo gbìyànjú láti wẹ̀ ọ́ mọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kò sì mọ́ kúrò nínú ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ rẹ, a kì yóò sì tún wẹ̀ ọ mọ́ kúrò nínú èérí rẹ, títí èmi yóò fi jẹ́ kí ìbínú mi balẹ̀ sórí rẹ̀. 14 “ ‘Èmi OLÚWA ni ó sọ ọ́, yóò sì ṣe, èmi yóò sì ṣe é. Èmi kì yóò padà sẹ́yìn; bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò dá sí i, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò yí ọkàn mi padà; gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ, àti gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ, ni wọn yóò dá ọ lẹ́jọ́, ni OLÚWA Olódùmarè wí.’ ” 15 Ọ̀rọ̀ OLÚWA sì tọ̀ mí wá pé: 16 “Ọmọ ènìyàn, kíyèsi i, mo mú ìfẹ́ ojú rẹ kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ, nípa lílù kan. Ṣùgbọ́n ìwọ kò gbọdọ̀ gbààwẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ sọkún, bẹ́ẹ̀ ni omijé ojú rẹ kò gbọdọ̀ kán sílẹ̀. 17 Má ṣe sọkún, má ṣe gbààwẹ̀ fún òkú. Wé ọ̀já sí orí rẹ, sì bọ bàtà sí ẹsẹ̀ rẹ, má ṣe bo ètè ìsàlẹ̀ rẹ, ma ṣe jẹ oúnjẹ tí àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ń jẹ gẹ́gẹ́ bí àṣà.” 18 Báyìí ni mo sọ̀rọ̀ fún àwọn ènìyàn ní òwúrọ̀, ní àṣálẹ́ ìyàwó mi sì kú. Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, mo ṣe bí a ti pàṣẹ fún mi. 19 Lẹ́yìn náà àwọn ènìyàn bi mí léèrè pé, “Ṣe o kò ni sọ fún wa ohun ti nǹkan wọ̀nyí ní láti ṣe pẹ̀lú wa?” 20 Mo sọ báyìí fún wọn pé, “Ọ̀rọ̀ OLÚWA tọ̀ mí wá wí pé: 21 Sọ fún ilé Israẹli, ‘Báyìí ní OLÚWA Olódùmarè wí: Kíyèsi i, èmi yóò sọ ibi mímọ́ mi di ibi àìmọ́ tayọ agbára yín, ìfẹ́ ojú yín, ìkáàánú yín, àti ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin tí ẹ̀yin fi sílẹ̀ sẹ́yìn yóò ṣubú nípa idà. 22 Ẹyin yóò sì ṣe bí mo ti ṣe. Ẹ̀yin kì yóò bo ìsàlẹ̀ ojú yín tàbí jẹ oúnjẹ ti àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ń jẹ gẹ́gẹ́ bí àṣà. 23 Ẹ̀yin yóò fi àwọn ọ̀já wé àwọn orí yín àti àwọn bàtà ni ẹsẹ̀ yín, ẹ̀yin kì yóò ṣọ̀fọ̀ tàbí sọkún, ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò ṣòfò dànù nítorí àwọn àìṣedéédéé yín, ẹ̀yin yóò sì máa kérora láàrín ara yín. 24 Esekiẹli yóò jẹ àmì fún un yín; ẹ̀yin yóò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí òun ti ṣe. Nígbà tí èyí bá ṣẹlẹ̀, ẹ̀yin yóò mọ̀ pé èmi ni OLÚWA Olódùmarè.’ 25 “Pẹ̀lúpẹ̀lú ìwọ, Ọmọ ènìyàn, kì yóò ha jẹ́ pé, ní ọjọ́ náà, nígbà ti mo bá gba agbára wọn, ayọ̀ wọn àti ògo wọn, ìfẹ́ ojú wọn, ohun tí wọn gbé ọkàn wọn lé, àti àwọn ọmọ ọkùnrin wọn pẹ̀lú àwọn ọmọ obìnrin wọn kúrò lọ́dọ̀ wọn, 26 ní ọjọ́ náà ẹni tí ó bá sálà yóò tọ̀ ọ́ wá láti sọ ìròyìn náà fún ọ. 27 Ní ọjọ́ náà ẹnu rẹ yóò sì ṣí; ìwọ yóò sọ̀rọ̀, ìwọ kì yóò sì yadi mọ́. Báyìí ìwọ yóò jẹ́ àmì fún wọn; wọn yóò sì mọ̀ pé èmi ní OLÚWA.”

In Other Versions

Ezekiel 24 in the ANGEFD

Ezekiel 24 in the ANTPNG2D

Ezekiel 24 in the AS21

Ezekiel 24 in the BAGH

Ezekiel 24 in the BBPNG

Ezekiel 24 in the BBT1E

Ezekiel 24 in the BDS

Ezekiel 24 in the BEV

Ezekiel 24 in the BHAD

Ezekiel 24 in the BIB

Ezekiel 24 in the BLPT

Ezekiel 24 in the BNT

Ezekiel 24 in the BNTABOOT

Ezekiel 24 in the BNTLV

Ezekiel 24 in the BOATCB

Ezekiel 24 in the BOATCB2

Ezekiel 24 in the BOBCV

Ezekiel 24 in the BOCNT

Ezekiel 24 in the BOECS

Ezekiel 24 in the BOGWICC

Ezekiel 24 in the BOHCB

Ezekiel 24 in the BOHCV

Ezekiel 24 in the BOHLNT

Ezekiel 24 in the BOHNTLTAL

Ezekiel 24 in the BOICB

Ezekiel 24 in the BOILNTAP

Ezekiel 24 in the BOITCV

Ezekiel 24 in the BOKCV

Ezekiel 24 in the BOKCV2

Ezekiel 24 in the BOKHWOG

Ezekiel 24 in the BOKSSV

Ezekiel 24 in the BOLCB

Ezekiel 24 in the BOLCB2

Ezekiel 24 in the BOMCV

Ezekiel 24 in the BONAV

Ezekiel 24 in the BONCB

Ezekiel 24 in the BONLT

Ezekiel 24 in the BONUT2

Ezekiel 24 in the BOPLNT

Ezekiel 24 in the BOSCB

Ezekiel 24 in the BOSNC

Ezekiel 24 in the BOTLNT

Ezekiel 24 in the BOVCB

Ezekiel 24 in the BPBB

Ezekiel 24 in the BPH

Ezekiel 24 in the BSB

Ezekiel 24 in the CCB

Ezekiel 24 in the CUV

Ezekiel 24 in the CUVS

Ezekiel 24 in the DBT

Ezekiel 24 in the DGDNT

Ezekiel 24 in the DHNT

Ezekiel 24 in the DNT

Ezekiel 24 in the ELBE

Ezekiel 24 in the EMTV

Ezekiel 24 in the ESV

Ezekiel 24 in the FBV

Ezekiel 24 in the FEB

Ezekiel 24 in the GGMNT

Ezekiel 24 in the GNT

Ezekiel 24 in the HARY

Ezekiel 24 in the HNT

Ezekiel 24 in the IRVA

Ezekiel 24 in the IRVB

Ezekiel 24 in the IRVG

Ezekiel 24 in the IRVH

Ezekiel 24 in the IRVK

Ezekiel 24 in the IRVM

Ezekiel 24 in the IRVM2

Ezekiel 24 in the IRVO

Ezekiel 24 in the IRVP

Ezekiel 24 in the IRVT

Ezekiel 24 in the IRVT2

Ezekiel 24 in the IRVU

Ezekiel 24 in the ISVN

Ezekiel 24 in the JSNT

Ezekiel 24 in the KAPI

Ezekiel 24 in the KBT1ETNIK

Ezekiel 24 in the KBV

Ezekiel 24 in the KJV

Ezekiel 24 in the KNFD

Ezekiel 24 in the LBA

Ezekiel 24 in the LBLA

Ezekiel 24 in the LNT

Ezekiel 24 in the LSV

Ezekiel 24 in the MAAL

Ezekiel 24 in the MBV

Ezekiel 24 in the MBV2

Ezekiel 24 in the MHNT

Ezekiel 24 in the MKNFD

Ezekiel 24 in the MNG

Ezekiel 24 in the MNT

Ezekiel 24 in the MNT2

Ezekiel 24 in the MRS1T

Ezekiel 24 in the NAA

Ezekiel 24 in the NASB

Ezekiel 24 in the NBLA

Ezekiel 24 in the NBS

Ezekiel 24 in the NBVTP

Ezekiel 24 in the NET2

Ezekiel 24 in the NIV11

Ezekiel 24 in the NNT

Ezekiel 24 in the NNT2

Ezekiel 24 in the NNT3

Ezekiel 24 in the PDDPT

Ezekiel 24 in the PFNT

Ezekiel 24 in the RMNT

Ezekiel 24 in the SBIAS

Ezekiel 24 in the SBIBS

Ezekiel 24 in the SBIBS2

Ezekiel 24 in the SBICS

Ezekiel 24 in the SBIDS

Ezekiel 24 in the SBIGS

Ezekiel 24 in the SBIHS

Ezekiel 24 in the SBIIS

Ezekiel 24 in the SBIIS2

Ezekiel 24 in the SBIIS3

Ezekiel 24 in the SBIKS

Ezekiel 24 in the SBIKS2

Ezekiel 24 in the SBIMS

Ezekiel 24 in the SBIOS

Ezekiel 24 in the SBIPS

Ezekiel 24 in the SBISS

Ezekiel 24 in the SBITS

Ezekiel 24 in the SBITS2

Ezekiel 24 in the SBITS3

Ezekiel 24 in the SBITS4

Ezekiel 24 in the SBIUS

Ezekiel 24 in the SBIVS

Ezekiel 24 in the SBT

Ezekiel 24 in the SBT1E

Ezekiel 24 in the SCHL

Ezekiel 24 in the SNT

Ezekiel 24 in the SUSU

Ezekiel 24 in the SUSU2

Ezekiel 24 in the SYNO

Ezekiel 24 in the TBIAOTANT

Ezekiel 24 in the TBT1E

Ezekiel 24 in the TBT1E2

Ezekiel 24 in the TFTIP

Ezekiel 24 in the TFTU

Ezekiel 24 in the TGNTATF3T

Ezekiel 24 in the THAI

Ezekiel 24 in the TNFD

Ezekiel 24 in the TNT

Ezekiel 24 in the TNTIK

Ezekiel 24 in the TNTIL

Ezekiel 24 in the TNTIN

Ezekiel 24 in the TNTIP

Ezekiel 24 in the TNTIZ

Ezekiel 24 in the TOMA

Ezekiel 24 in the TTENT

Ezekiel 24 in the UBG

Ezekiel 24 in the UGV

Ezekiel 24 in the UGV2

Ezekiel 24 in the UGV3

Ezekiel 24 in the VBL

Ezekiel 24 in the VDCC

Ezekiel 24 in the YALU

Ezekiel 24 in the YAPE

Ezekiel 24 in the YBVTP

Ezekiel 24 in the ZBP