1 Corinthians 9 (BOYCB)

1 Èmi kò ha ni òmìnira bí? Èmi kò ha ń ṣe aposteli bí? Èmi kò ha ti rí Jesu Olúwa bí? Ẹ̀yìn ha kọ́ ní èrè iṣẹ́ mi nínú Olúwa bí? 2 Ní ìrònú àwọn ẹlòmíràn, èmi kì í ṣe aposteli. Dájúdájú aposteli ni mo jẹ́ fún un yín, tí n kì bá ṣe fún àwọn ẹlòmíràn. Nítorí èdìdì iṣẹ́ aposteli mi ni ẹ̀yin jẹ́ nínú Olúwa. 3 Èyí ni ìdáhùn mi sí àwọn tí ń béèrè ẹ̀tọ́ aposteli mi. 4 Ṣé a kò ní ẹ̀tọ́ láti máa jẹ àti láti máa mu bí? 5 Ṣé àwa kò ní ẹ̀tọ́ láti máa mú ìyàwó tí í ṣe onígbàgbọ́ káàkiri gẹ́gẹ́ bí àwọn aposteli mìíràn? Àti bí arákùnrin Olúwa, àti Kefa. 6 Ṣé èmi nìkan àti Barnaba, àwa kò ha ní agbára láti máa ṣiṣẹ́ bọ́ ara wa ni? 7 Ta ni ó ṣíṣẹ́ ológun tí ó sanwó ara rẹ̀? Ta ní gbin ọgbà àjàrà tí kì í jẹ nínú èso rẹ̀? Tàbí ta ní ń bọ ọ̀wọ́ ẹran tí kì í sí ì jẹ nínú wàrà ọ̀wọ́ ẹran? 8 Èmi ha sọ nǹkan wọ̀nyí bí ènìyàn? Tàbí òfin kò wí bákan náà bì? 9 Nítorí nínú òfin tí Ọlọ́run fún Mose, ni a tí kọ ọ́ pé, “Ìwọ kò gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu.” Ǹjẹ́ màlúù ni Ọlọ́run n ṣe ìtọ́jú rẹ̀ bi? 10 Dájúdájú ó sọ eléyìí fún wa pé, nítorí wa ni a ṣe kọ̀wé yìí kí ẹni tí ń tulẹ̀ lè máa tulẹ̀ ní ìrètí àti ẹni tí ń pakà lè ni ìrètí láti ní ìpín nínú ìkórè. 11 Bí àwa ti fún irúgbìn ohun ti ẹ̀mí sínú ọkàn yín, ohun ńlá ha ni bí àwa ó ba ká ohun ti yín tí ṣe ti ara? 12 Bí àwọn ẹlòmíràn bá ní ẹ̀tọ́ tí ìrànlọ́wọ́ sì wá láti ọ̀dọ̀ yín, àwa ha kọ́ ni ó tọ́ sí jù?Ṣùgbọ́n àwa kò lo agbára yìí ṣùgbọ́n àwa faradà ohun gbogbo, kí àwa má ba à ṣe ìdènà fún ìyìnrere Kristi. 13 Ǹjẹ́ ó yé e yín pé Ọlọ́run sọ fún àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ nínú tẹmpili pé kí wọ́n mú oúnjẹ tàbí àwọn ẹ̀bùn tí wọ́n mú wá fún òun, láti fi ṣe ìtọ́jú ara wọn? Àti àwọn tí ń dúró tí pẹpẹ wọn a máa ṣe àjọpín pẹ̀lú pẹpẹ. 14 Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni Olúwa ti fi àṣẹ lélẹ̀ pé, àwọn tí ń wàásù ìyìnrere kí wọn sì máa jẹ́ nípa ìyìnrere. 15 Síbẹ̀síbẹ̀ n kò ì tí ì lo irú àwọn ẹ̀tọ́ wọ̀nyí rí. Bẹ́ẹ̀ ni èmi kò sì kọ ìwé yìí láti fi sọ fún un yín pé, mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ sí í gbà irú nǹkan bẹ̀ ẹ́ lọ́wọ́ yín. Kí a sọ òtítọ́, ó sàn fún mi láti kú sínú ebi ju pé kí n sọ ògo tí mo ní láti wàásù nù. 16 Nítorí pé bí mo ti ń wàásù ìyìnrere, kì í ṣe ohun tí mo lè máa ṣògo lè. Èmi kò tilẹ̀ le è ṣe é ní, kí a tilẹ̀ sọ pé mo fẹ́ kọ̀ ọ́ sílẹ̀. Ègbé ni fún mi tí mo bá kọ̀ láti wàásù ìyìnrere. 17 Tó bá jẹ́ pé mò ń wàásù tinútinú mi, mo ní èrè kan, ṣùgbọ́n tí ń kò bá ṣe tinútinú mi, a ti fi iṣẹ́ ìríjú lé mi lọ́wọ́. 18 Ní irú ipò báyìí, kín ni ẹ rò pé yóò jẹ èrè mi ni láti jẹ́? Èrè mi ní àgbàyanu ayọ̀ tí mo ń rí gbà nípa ìwàásù ìyìnrere láìgba owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, láìbéèrè ẹ̀tọ́ mi lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni. 19 Bí mo ti jẹ́ òmìnira tí ń kò sì darapọ̀ mọ́ ẹnikẹ́ni, mo sọ ara mi di ẹrú lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn, láti lè jèrè ọ̀pọ̀lọpọ̀ sí i. 20 Nígbà tí mó wà lọ́dọ̀ àwọn Júù, mo dàbí ọ̀kan nínú wọn, kí wọn ba à lè tẹ́tí sí ìwàásù ìyìnrere mi àti ki n le jèrè wọn fún Kristi. Nígbà tí mo bá wà láàrín àwọn tó wà lábẹ́ òfin èmi kì í bá wọn jiyàn rárá (bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé èmi kò sí lábẹ́ òfin), kí èmi lè jèrè àwọn ti ń bẹ lábẹ́ òfin. 21 Nígbà tí mo bá wà láàrín àwọn tí kò sí lábẹ́ òfin, èmi náà yóò dàbí ẹni tí kò sí lábẹ́ òfin (èmi kì í ṣe aláìlófin sí Ọlọ́run, ṣùgbọ́n èmí ń bẹ lábẹ́ òfin Kristi), kí èmi le jèrè àwọn tí kò sí lábẹ́ òfin. 22 Nígbà tí mo bá wà láàrín àwọn aláìlera, èmi náà yóò di aláìlera, kí èmi lé jèrè àwọn aláìlera. Mo di ohun gbogbo fún gbogbo ènìyàn, kí èmi ba à lè gba díẹ̀ là lábẹ́ bí ó ti wù kí ó rí. 23 Èmi sì ń ṣe ohun gbogbo nítorí ti ìyìnrere, kí èmi kí ó lè jẹ́ alábápín nínú rẹ̀ pẹ̀lú yín. 24 Ẹ̀yin kò mọ̀ pé, olúkúlùkù ẹni tí ó ní ipa nínú eré ìje ni ó máa ń sáré, ṣùgbọ́n ẹnìkan ṣoṣo ni ń gba ipò ẹ̀bùn tí ó ga jù. Nítorí náà, ẹ sá eré ìje yín kí ẹ ba à le borí. 25 Gbogbo ẹni tí ó ń sáré ìje a máa lọ nínú ìsẹ́ra-ẹni tí ó lágbára. Wọ́n ń ṣe èyí láti gba adé ìdíbàjẹ́. Ṣùgbọ́n àwa ń sá eré ìje tiwa láti fi gba adé ọ̀run àìdíbàjẹ́ láéláé. 26 Nítorí náà, mo ń sá eré ìje lọ sójú àmì, kì í ṣe bí ẹni ti kò dá lójú. Mò ń jà kí n lè borí, kì í ṣe bí ẹni tí ń bá afẹ́fẹ́ jà. 27 Ṣùgbọ́n èmi ń kó ara mi ní ìjánu, mo sì ń mú un wá sí abẹ́ ìtẹríba, pé lẹ́yìn tí mo ti wàásù fún àwọn ẹlòmíràn, nítorí ohunkóhun, kí èmi fún rara mi má ṣe di ẹni ìtanù fún ẹ̀bùn náà.

In Other Versions

1 Corinthians 9 in the ANGEFD

1 Corinthians 9 in the ANTPNG2D

1 Corinthians 9 in the AS21

1 Corinthians 9 in the BAGH

1 Corinthians 9 in the BBPNG

1 Corinthians 9 in the BBT1E

1 Corinthians 9 in the BDS

1 Corinthians 9 in the BEV

1 Corinthians 9 in the BHAD

1 Corinthians 9 in the BIB

1 Corinthians 9 in the BLPT

1 Corinthians 9 in the BNT

1 Corinthians 9 in the BNTABOOT

1 Corinthians 9 in the BNTLV

1 Corinthians 9 in the BOATCB

1 Corinthians 9 in the BOATCB2

1 Corinthians 9 in the BOBCV

1 Corinthians 9 in the BOCNT

1 Corinthians 9 in the BOECS

1 Corinthians 9 in the BOGWICC

1 Corinthians 9 in the BOHCB

1 Corinthians 9 in the BOHCV

1 Corinthians 9 in the BOHLNT

1 Corinthians 9 in the BOHNTLTAL

1 Corinthians 9 in the BOICB

1 Corinthians 9 in the BOILNTAP

1 Corinthians 9 in the BOITCV

1 Corinthians 9 in the BOKCV

1 Corinthians 9 in the BOKCV2

1 Corinthians 9 in the BOKHWOG

1 Corinthians 9 in the BOKSSV

1 Corinthians 9 in the BOLCB

1 Corinthians 9 in the BOLCB2

1 Corinthians 9 in the BOMCV

1 Corinthians 9 in the BONAV

1 Corinthians 9 in the BONCB

1 Corinthians 9 in the BONLT

1 Corinthians 9 in the BONUT2

1 Corinthians 9 in the BOPLNT

1 Corinthians 9 in the BOSCB

1 Corinthians 9 in the BOSNC

1 Corinthians 9 in the BOTLNT

1 Corinthians 9 in the BOVCB

1 Corinthians 9 in the BPBB

1 Corinthians 9 in the BPH

1 Corinthians 9 in the BSB

1 Corinthians 9 in the CCB

1 Corinthians 9 in the CUV

1 Corinthians 9 in the CUVS

1 Corinthians 9 in the DBT

1 Corinthians 9 in the DGDNT

1 Corinthians 9 in the DHNT

1 Corinthians 9 in the DNT

1 Corinthians 9 in the ELBE

1 Corinthians 9 in the EMTV

1 Corinthians 9 in the ESV

1 Corinthians 9 in the FBV

1 Corinthians 9 in the FEB

1 Corinthians 9 in the GGMNT

1 Corinthians 9 in the GNT

1 Corinthians 9 in the HARY

1 Corinthians 9 in the HNT

1 Corinthians 9 in the IRVA

1 Corinthians 9 in the IRVB

1 Corinthians 9 in the IRVG

1 Corinthians 9 in the IRVH

1 Corinthians 9 in the IRVK

1 Corinthians 9 in the IRVM

1 Corinthians 9 in the IRVM2

1 Corinthians 9 in the IRVO

1 Corinthians 9 in the IRVP

1 Corinthians 9 in the IRVT

1 Corinthians 9 in the IRVT2

1 Corinthians 9 in the IRVU

1 Corinthians 9 in the ISVN

1 Corinthians 9 in the JSNT

1 Corinthians 9 in the KAPI

1 Corinthians 9 in the KBT1ETNIK

1 Corinthians 9 in the KBV

1 Corinthians 9 in the KJV

1 Corinthians 9 in the KNFD

1 Corinthians 9 in the LBA

1 Corinthians 9 in the LBLA

1 Corinthians 9 in the LNT

1 Corinthians 9 in the LSV

1 Corinthians 9 in the MAAL

1 Corinthians 9 in the MBV

1 Corinthians 9 in the MBV2

1 Corinthians 9 in the MHNT

1 Corinthians 9 in the MKNFD

1 Corinthians 9 in the MNG

1 Corinthians 9 in the MNT

1 Corinthians 9 in the MNT2

1 Corinthians 9 in the MRS1T

1 Corinthians 9 in the NAA

1 Corinthians 9 in the NASB

1 Corinthians 9 in the NBLA

1 Corinthians 9 in the NBS

1 Corinthians 9 in the NBVTP

1 Corinthians 9 in the NET2

1 Corinthians 9 in the NIV11

1 Corinthians 9 in the NNT

1 Corinthians 9 in the NNT2

1 Corinthians 9 in the NNT3

1 Corinthians 9 in the PDDPT

1 Corinthians 9 in the PFNT

1 Corinthians 9 in the RMNT

1 Corinthians 9 in the SBIAS

1 Corinthians 9 in the SBIBS

1 Corinthians 9 in the SBIBS2

1 Corinthians 9 in the SBICS

1 Corinthians 9 in the SBIDS

1 Corinthians 9 in the SBIGS

1 Corinthians 9 in the SBIHS

1 Corinthians 9 in the SBIIS

1 Corinthians 9 in the SBIIS2

1 Corinthians 9 in the SBIIS3

1 Corinthians 9 in the SBIKS

1 Corinthians 9 in the SBIKS2

1 Corinthians 9 in the SBIMS

1 Corinthians 9 in the SBIOS

1 Corinthians 9 in the SBIPS

1 Corinthians 9 in the SBISS

1 Corinthians 9 in the SBITS

1 Corinthians 9 in the SBITS2

1 Corinthians 9 in the SBITS3

1 Corinthians 9 in the SBITS4

1 Corinthians 9 in the SBIUS

1 Corinthians 9 in the SBIVS

1 Corinthians 9 in the SBT

1 Corinthians 9 in the SBT1E

1 Corinthians 9 in the SCHL

1 Corinthians 9 in the SNT

1 Corinthians 9 in the SUSU

1 Corinthians 9 in the SUSU2

1 Corinthians 9 in the SYNO

1 Corinthians 9 in the TBIAOTANT

1 Corinthians 9 in the TBT1E

1 Corinthians 9 in the TBT1E2

1 Corinthians 9 in the TFTIP

1 Corinthians 9 in the TFTU

1 Corinthians 9 in the TGNTATF3T

1 Corinthians 9 in the THAI

1 Corinthians 9 in the TNFD

1 Corinthians 9 in the TNT

1 Corinthians 9 in the TNTIK

1 Corinthians 9 in the TNTIL

1 Corinthians 9 in the TNTIN

1 Corinthians 9 in the TNTIP

1 Corinthians 9 in the TNTIZ

1 Corinthians 9 in the TOMA

1 Corinthians 9 in the TTENT

1 Corinthians 9 in the UBG

1 Corinthians 9 in the UGV

1 Corinthians 9 in the UGV2

1 Corinthians 9 in the UGV3

1 Corinthians 9 in the VBL

1 Corinthians 9 in the VDCC

1 Corinthians 9 in the YALU

1 Corinthians 9 in the YAPE

1 Corinthians 9 in the YBVTP

1 Corinthians 9 in the ZBP