Isaiah 5 (BOYCB)

1 Èmi yóò kọrin fún ẹni tí mo fẹ́rànorin kan nípa ọgbà àjàrà rẹ̀.Olùfẹ́ mi ní ọgbà àjàrà kanní ẹ̀gbẹ́ òkè ẹlẹ́tù lójú. 2 Ó tu ilẹ̀ rẹ̀, ó ṣa òkúta ibẹ̀ kúròó sì gbin àyànfẹ́ àjàrà sí i.Ó kọ́ ilé ìṣọ́ sí inú rẹ̀ó sì ṣe ìfúntí kan síbẹ̀ pẹ̀lú.Lẹ́yìn náà, ó ń retí èso àjàrà dáradára,ṣùgbọ́n èso búburú ni ó ti ibẹ̀ wá. 3 “Ní ìsinsin yìí ẹ̀yin olùgbé Jerusalẹmuàti ẹ̀yin ènìyàn Judaẹ ṣe ìdájọ́ láàrín èmi àtiọgbà àjàrà mi. 4 Kín ni ó kù tí n ò bá túnṣe sí ọgbà àjàrà mi.Ju èyí tí mo ti ṣe lọ?Nígbà tí mo ń wá èso dáradára,èéṣe tí ó fi so kíkan? 5 Ní ìsinsin yìí, èmi yóò wí fún ọohun tí n ó ṣe sí ọgbà àjàrà mi.Èmi yóò gé igi inú rẹ̀ kúrò,a ó sì pa á run,Èmi yóò wó ògiri rẹ̀ lulẹ̀yóò sì di ìtẹ̀mọ́lẹ̀. 6 Èmi yóò sì sọ ọ́ di ahoroláì kọ ọ́ láì ro ó,ẹ̀wọ̀n àti ẹ̀gún ni yóò hù níbẹ̀.Èmi yóò sì pàṣẹ fún kurukuruláti má ṣe rọ̀jò sórí i rẹ̀.” 7 Ọgbà àjàrà OLÚWA àwọn ọmọ-ogunni ilé Israẹliàwọn ọkùnrin Judasì ni àyànfẹ́ ọgbà rẹ̀.Ó retí ìdájọ́ ẹ̀tọ́ ṣùgbọ́n, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ni ó rí.Òun ń retí òdodo ṣùgbọ́n ó gbọ́ ẹkún ìpayínkeke. 8 Ègbé ni fún àwọn tí ń kọ́lé mọ́létí ó sì ń ra ilẹ̀ mọ́lẹ̀tó bẹ́ẹ̀ tí ààyè kò ṣẹ́kùtí ó sì nìkan gbé lórí ilẹ̀. 9 OLÚWA àwọn ọmọ-ogun ti sọ ọ́ sí mi létí:“Ó dájú pé àwọn ilé ńlá ńláyóò di ahoro, àwọn ilé dáradára yóò wà láìní olùgbé. 10 Ọgbà àjàrà sáré oko mẹ́wàá yóò múìkòkò wáìnì kan wá,nígbà tí òsùwọ̀n homeri kan yóò múagbọ̀n irúgbìn kan wá.” 11 Ègbé ni fún àwọn tí wọ́n dìdení kùtùkùtù òwúrọ̀láti lépa ọtí líle,tí wọ́n sì mu ún títí alẹ́ fi lẹ́títí wọ́n fi gbinájẹ pẹ̀lú wáìnì. 12 Wọ́n ní dùùrù àti ohun èlò orin olókùn níbi àsè wọn,ṣaworo òun fèrè àti wáìnì,ṣùgbọ́n wọn kò ka iṣẹ́ OLÚWA sí,wọn kò sí bọ̀wọ̀ fún iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀. 13 Nítorí náà àwọn ènìyàn mi yóò lọ sí ìgbèkùnnítorí òye kò sí fún wọn,ebi ni yóò pa àwọn ọlọ́lá wọn kú;ẹgbàágbèje wọn ni òǹgbẹ yóò sì gbẹ. 14 Nítorí náà isà òkú ti ń dátọ́mì gidigidi,ó sì ti ya ẹnu rẹ̀ sílẹ̀ gbagada,nínú rẹ̀ ni àwọn gbajúmọ̀ àti mẹ̀kúnnù yóò sọ̀kalẹ̀ sípẹ̀lú ọlá àti ògo wọn. 15 Báyìí, ènìyàn yóò di ìrẹ̀sílẹ̀àti ọmọ ènìyàn ni a sọ di onírẹ̀lẹ̀ojú agbéraga ni a sì rẹ̀ sílẹ̀. 16 Ṣùgbọ́n OLÚWA àwọn ọmọ-ogun ni a ó gbéga nípa ẹ̀tọ́ rẹ̀,Ọlọ́run ẹni mímọ́ yóò sì fi ara rẹ̀ hàn ní mímọ́ nípa òdodo rẹ̀. 17 Nígbà náà ni àwọn àgùntàn yóò máa jẹ́ ko ní ibùgbé e wọn,àwọn ọ̀dọ́-àgùntàn yóò máa jẹ nínú ahoro àwọn ọlọ́rọ̀. 18 Ègbé ni fún àwọn tí ń fi ohun asán fa ẹ̀ṣẹ̀,àti àwọn tí o dàbí ẹni pé wọ́n ń fi okùn kẹ̀kẹ́ ẹ̀sìn fa ẹsẹ̀, 19 sí àwọn tí ó sọ pé, “Jẹ́ kí Ọlọ́run ṣe kíákíá,jẹ́ kí ó yára ṣiṣẹ́ rẹ̀ kí a lè rí i,jẹ́ kí ó súnmọ́ bíjẹ́ kí ètò ẹni mímọ́ Israẹli kí ó dé,kí àwa kí ó le mọ̀ ọ́n.” 20 Ègbé ni fún àwọn tí ń pe ibi ní rere, àti rere ní ibi,tí ń fi òkùnkùn ṣe ìmọ́lẹ̀ àti ìmọ́lẹ̀ ṣe òkùnkùn,tí ń fi ìkorò ṣe adùn àti adùn ṣe ìkorò. 21 Ègbé ni fún àwọn tí ó gbọ́n lójú ara wọntí wọ́n jáfáfá lójú ara wọn. 22 Ègbé ni fún àwọn akọni nínú wáìnì mímuàti àwọn akíkanjú nínú àdàlú ọtí, 23 tí wọ́n dá ẹlẹ́bi sílẹ̀ nítorí àbẹ̀tẹ́lẹ̀,tí wọn sì du aláre ní ẹ̀tọ́. 24 Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bí ahọ́n iná ṣe ń jó àgékù koríko runàti bí koríko ṣe rẹlẹ̀ wẹ̀sì nínú iná,bẹ́ẹ̀ ni egbò wọn yóò jẹràtí òdodo wọn yóò sì fẹ́ lọ bí eruku:nítorí pé wọ́n ti kọ òfin OLÚWA àwọn ọmọ-ogun sílẹ̀wọ́n sì gan ọ̀rọ̀ Ẹni mímọ́ Israẹli. 25 Nítorí náà, ìbínú OLÚWA gbóná si àwọn ènìyàn rẹ̀,ó ti gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè, ó sì lù wọ́n bolẹ̀.Àwọn òkè sì wárìrì,òkú wọn sì dàbí ààtàn ní àárín ìgboro.Pẹ̀lú gbogbo èyí, ìbínú rẹ̀ kò yí kúrò,ṣùgbọ́n ọ̀wọ́ rẹ̀ sì ná jáde síbẹ̀. 26 Yóò sì gbé ọ̀págun sókè sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ó jìnnà,yóò sì kọ sí wọn tí ó wà ní ìpẹ̀kun ilẹ̀.Sì kíyèsi, wọ́n yóò yára wá kánkán. 27 Kò sí ẹni tí yóò rẹ̀ nínú wọn, tàbí tí yóò kọsẹ̀,kò sí ẹni tí yóò tòògbé tàbí tí yóò sùn;bẹ́ẹ̀ ni àmùrè ẹ̀gbẹ́ wọn kì yóò tú,bẹ́ẹ̀ ni okùn sálúbàtà wọn kì yóò ja. 28 Àwọn ọfà wọn múná,gbogbo ọrun wọn sì le;pátákò àwọn ẹṣin wọn le bí òkúta akọ,àwọn àgbá kẹ̀kẹ́ wọn sì dàbí ìjì líle. 29 Bíbú wọn dàbí tí kìnnìún,wọ́n bú bí ẹgbọrọ kìnnìún,wọ́n ń kọ bí wọ́n ti di ẹran ọdẹ wọn mútí wọn sì gbé e lọ láìsí ẹni tí yóò gbà á là. 30 Ní ọjọ́ náà, wọn yóò hó lé e lórígẹ́gẹ́ bí i rírú omi Òkun.Bí ènìyàn bá sì wo ilẹ̀,yóò rí òkùnkùn àti ìbànújẹ́;pẹ̀lúpẹ̀lú ìmọ́lẹ̀ yóò di òkùnkùn pẹ̀lú kurukuru rẹ̀.

In Other Versions

Isaiah 5 in the ANGEFD

Isaiah 5 in the ANTPNG2D

Isaiah 5 in the AS21

Isaiah 5 in the BAGH

Isaiah 5 in the BBPNG

Isaiah 5 in the BBT1E

Isaiah 5 in the BDS

Isaiah 5 in the BEV

Isaiah 5 in the BHAD

Isaiah 5 in the BIB

Isaiah 5 in the BLPT

Isaiah 5 in the BNT

Isaiah 5 in the BNTABOOT

Isaiah 5 in the BNTLV

Isaiah 5 in the BOATCB

Isaiah 5 in the BOATCB2

Isaiah 5 in the BOBCV

Isaiah 5 in the BOCNT

Isaiah 5 in the BOECS

Isaiah 5 in the BOGWICC

Isaiah 5 in the BOHCB

Isaiah 5 in the BOHCV

Isaiah 5 in the BOHLNT

Isaiah 5 in the BOHNTLTAL

Isaiah 5 in the BOICB

Isaiah 5 in the BOILNTAP

Isaiah 5 in the BOITCV

Isaiah 5 in the BOKCV

Isaiah 5 in the BOKCV2

Isaiah 5 in the BOKHWOG

Isaiah 5 in the BOKSSV

Isaiah 5 in the BOLCB

Isaiah 5 in the BOLCB2

Isaiah 5 in the BOMCV

Isaiah 5 in the BONAV

Isaiah 5 in the BONCB

Isaiah 5 in the BONLT

Isaiah 5 in the BONUT2

Isaiah 5 in the BOPLNT

Isaiah 5 in the BOSCB

Isaiah 5 in the BOSNC

Isaiah 5 in the BOTLNT

Isaiah 5 in the BOVCB

Isaiah 5 in the BPBB

Isaiah 5 in the BPH

Isaiah 5 in the BSB

Isaiah 5 in the CCB

Isaiah 5 in the CUV

Isaiah 5 in the CUVS

Isaiah 5 in the DBT

Isaiah 5 in the DGDNT

Isaiah 5 in the DHNT

Isaiah 5 in the DNT

Isaiah 5 in the ELBE

Isaiah 5 in the EMTV

Isaiah 5 in the ESV

Isaiah 5 in the FBV

Isaiah 5 in the FEB

Isaiah 5 in the GGMNT

Isaiah 5 in the GNT

Isaiah 5 in the HARY

Isaiah 5 in the HNT

Isaiah 5 in the IRVA

Isaiah 5 in the IRVB

Isaiah 5 in the IRVG

Isaiah 5 in the IRVH

Isaiah 5 in the IRVK

Isaiah 5 in the IRVM

Isaiah 5 in the IRVM2

Isaiah 5 in the IRVO

Isaiah 5 in the IRVP

Isaiah 5 in the IRVT

Isaiah 5 in the IRVT2

Isaiah 5 in the IRVU

Isaiah 5 in the ISVN

Isaiah 5 in the JSNT

Isaiah 5 in the KAPI

Isaiah 5 in the KBT1ETNIK

Isaiah 5 in the KBV

Isaiah 5 in the KJV

Isaiah 5 in the KNFD

Isaiah 5 in the LBA

Isaiah 5 in the LBLA

Isaiah 5 in the LNT

Isaiah 5 in the LSV

Isaiah 5 in the MAAL

Isaiah 5 in the MBV

Isaiah 5 in the MBV2

Isaiah 5 in the MHNT

Isaiah 5 in the MKNFD

Isaiah 5 in the MNG

Isaiah 5 in the MNT

Isaiah 5 in the MNT2

Isaiah 5 in the MRS1T

Isaiah 5 in the NAA

Isaiah 5 in the NASB

Isaiah 5 in the NBLA

Isaiah 5 in the NBS

Isaiah 5 in the NBVTP

Isaiah 5 in the NET2

Isaiah 5 in the NIV11

Isaiah 5 in the NNT

Isaiah 5 in the NNT2

Isaiah 5 in the NNT3

Isaiah 5 in the PDDPT

Isaiah 5 in the PFNT

Isaiah 5 in the RMNT

Isaiah 5 in the SBIAS

Isaiah 5 in the SBIBS

Isaiah 5 in the SBIBS2

Isaiah 5 in the SBICS

Isaiah 5 in the SBIDS

Isaiah 5 in the SBIGS

Isaiah 5 in the SBIHS

Isaiah 5 in the SBIIS

Isaiah 5 in the SBIIS2

Isaiah 5 in the SBIIS3

Isaiah 5 in the SBIKS

Isaiah 5 in the SBIKS2

Isaiah 5 in the SBIMS

Isaiah 5 in the SBIOS

Isaiah 5 in the SBIPS

Isaiah 5 in the SBISS

Isaiah 5 in the SBITS

Isaiah 5 in the SBITS2

Isaiah 5 in the SBITS3

Isaiah 5 in the SBITS4

Isaiah 5 in the SBIUS

Isaiah 5 in the SBIVS

Isaiah 5 in the SBT

Isaiah 5 in the SBT1E

Isaiah 5 in the SCHL

Isaiah 5 in the SNT

Isaiah 5 in the SUSU

Isaiah 5 in the SUSU2

Isaiah 5 in the SYNO

Isaiah 5 in the TBIAOTANT

Isaiah 5 in the TBT1E

Isaiah 5 in the TBT1E2

Isaiah 5 in the TFTIP

Isaiah 5 in the TFTU

Isaiah 5 in the TGNTATF3T

Isaiah 5 in the THAI

Isaiah 5 in the TNFD

Isaiah 5 in the TNT

Isaiah 5 in the TNTIK

Isaiah 5 in the TNTIL

Isaiah 5 in the TNTIN

Isaiah 5 in the TNTIP

Isaiah 5 in the TNTIZ

Isaiah 5 in the TOMA

Isaiah 5 in the TTENT

Isaiah 5 in the UBG

Isaiah 5 in the UGV

Isaiah 5 in the UGV2

Isaiah 5 in the UGV3

Isaiah 5 in the VBL

Isaiah 5 in the VDCC

Isaiah 5 in the YALU

Isaiah 5 in the YAPE

Isaiah 5 in the YBVTP

Isaiah 5 in the ZBP